Powered By Blogger

Subscribe Now: RSS feed

Friday, June 28, 2013

World Ṣàngó Festival 2013



Ọba Ọ̀yọ́, ọba Làmídì Adéyẹmí kẹ́ta, n pè ọ́ sí ayẹyẹ ọdún Ṣàngó àgbáyé tí yóò wáyé nínú oṣù Ògún, tẹ ìpolówó òkè yìí kí ó darí rẹ.

Gbogbo yín lapé o!!!

The king of Ọ̀yọ́, ba Làmídì Adéymí 111 invites the world to the World Ṣàngó Festival in August, 2013. Click the above video to see the commercial.

Come one, come all!!!


Friday, June 14, 2013

Fi Èdè Yorùbá Kọ́ Ọmọọ̀ Rẹ (Teach Your Child Yorùbá Language)

Lánàá òde yìí, ẹgbẹ́ agbóhùnsafẹ́fẹ́ lédè Yoòbá pé ìpàdé àpérò, ìjíròrò ìṣe, àṣà Yorùbá, orí ọ̀rọ̀ ìjókó náà kò sì kọjá ohun tí a lè ṣe, ọ̀nà tí a lè gbà gbé èdè àṣà, ìṣe ìbílẹ̀ wa lárugẹ. 


The Yorùbá Broadcasters Association, Lagos state organized a seminar on reviving the Yorùbá language in our homes.


Ọ̀pọ̀ ọmọ Yoòbá àtàtà, àwọn lọ́balọ́ba, èèyàn jànkàn-jànkàn ló péjọ síbi ìpàdé yìí láti gbé àṣà baba-ńláa wa ga. Àwọn àgbàgbà bíi baba Ẹlẹ́buìbọn, ògbóntàgi ọ̀yàwòrán èré orí-ìtàgé Túndé Kìlání, olóyè Gàní Adams àti àwọn ọmọ Yorùbá réré l'ó péjúpésẹ̀. Wọ́n ṣa àwọn òbí láì yọ̀ alágbàtọ́ sílẹ̀ lábẹ ọ̀rọ̀, wọ́n wí fún wọn pé ó kúdíẹ̀káàtó kí ọmọ káàárọ̀-o-ò-jíire málè fọ èdè bàba rẹ̀. 


Various sons and daughters of Yoruba land were in attendance; Lai Mohammed, Tunde Kilani, Yemi Elebuibon, Gani Adams and others.


Ìwádí fi hàn pé bí ó ba e díẹ̀, èdè Yorùbá a pare, k'Èlédùà máj a ríi.  Lá ní láti fwọ́sowọ́pọ̀ wá nǹkan e kí èdè wa má báa gb bí i odò, kí a má gbàgbé orísun wa.

Researchers claim that in years to come, the Yoruba language will be extinct. We must therefore collectively endeavour not to let it die.

Àfi kọ́mọ Yoòbá máà f'èèbó bi ọ̀pẹ́ẹ̀rẹ̀. Alàgbà Láì Mòhammẹ̀d ti ẹgbẹ́ òṣèlú ACN pàápàá gbà àwọn òbí nimọ̀ràn láti fi èdè, àṣà ìṣe ilé wa kọ́, tọ́ àti wo àwọn èwe wa torí àwọn ọmọ wọ̀nyí ni yí ó kù nílé bí àgbà ilé bá filẹ̀ ṣaṣọ bọra, àwọn ni kò ní jẹ́ kílé dahoro. 


Instead of speaking more in Yoruba, our children speaks English than the former, whereas some don't even know how to speak because their parents do not teach or speak with them in Yoruba language. Chief Lai Mohammed implored parents to speak and teach the Yoruba culture to their wards.

Torí náà, ó ṣe kókó, ó ṣe pàtàkì kí àwọn ọmọ àti àrọ́mọdọ́mọ wa gbọ́ Yoòbá kí èdè baba ńláa wa Oòduà, Ọ̀rànmíyàn, àti àwọn àgbàgbà ilẹ̀ kú-oótù-oòjíire má bá à di ohun ìgbàkánnì, ohun ìgbàgbé, òyìnbó là á ńtẹ̀lé gọ̀ṣúgọ̀ṣú a gbàgbé pé a kí í ṣe òyìnbó a si le dabi won. 

Chinua Achebe has said, "my people no longer act as one..." why? because things has fallen apart, we all want to act and be like the whites neglecting the real-self whereas this is not possible. We should stop following them like zombies.

Ọ̀rọ̀ yìí kànwá gbògbògbò, ó kandandan kí ọmọ Odùduà mọ òwe, ìṣe, iṣẹ́ àti gbogbo nǹkan tó rọ̀mọ́ àṣà Yorùbá. A kúkú ní báwọn wí bíkòṣe àwọn òyìnbó ọlọ́gbọ́n àrékéreké tí ó sa gbogbo ipá láti pa ìran Yorùbá rẹ́ lórílẹ̀-èdè ayé. Àti pé, ó yẹ kí ilé-ìwé máà fi èdè àbínibí kọ́ àwọn akẹ́kọ́ọ̀ọ́ láti jẹ́léósimi alákọ̀bẹ̀rẹ̀ títí dé ilé ẹ̀kọ́ gíga Yunifásitì, èyí á jẹ́ kí akẹ́kọ́ọ̀ọ́ mọ ìgbéayée wọn gẹ́gẹ́ bí alágbẹ̀dẹ ṣe mọ Ògún.  

Brethren, it is our responsibility as bonnafide sons and daughters of Oduduwa to train our child in the way of the Yorùbá culture and tradition. The educational curriculum should accommodate teaching all subjects, courses in Yorùbá language from elementary to higher institution.

Toò, tèmi tìrẹ, m Oòduà tkàntkàn, ìṣẹ̀ṣe làgbà, ọmọàlè ní ń f'ọwọ́ òsì júwe ilé Bàbá rẹ̀, kí Yorùbá má bàá kú dọwọ́ wa ooooo!!!  

To this end, tradition is key and paramount, only a bastard points to his father house with his left hand. True sons of Oòduà, the onus lie on all Yorùbá to keep the Yorùbá heritage alive for the future generation.


Do you understand Yorùbá? Do you speak it well? Watch this little girl as she speaks the Yorùbá language Fi Èdè Yorùbá Kọ́ Ọmọọ̀ Rẹ

Click and subscribe - www.youtube.com/yobamoodua 


eun :)

Check out www.yobamoodua.org for more on Yorùbá education and information.

Tuesday, June 11, 2013

Mọ̀SHOOD KÁṣÌMÁAWÒÓ ỌLÁWÁLÉ ÀBÍọ́LA - OGUN ỌDÚN (June 12, 1993)

 On the 12th of June 1993, Moshood Kasimawo Olawale Abiola contested for the post of the Nigerian Presidency under the Social Democratic Party (SDP) which he won but his election was annulled and the count was given to someone else. 

This decision by the powerful ones in government led to an uproar in the cities especially in Lagos State, i can remember that rogues burning tires and causing mayhem snatched my mother's handbag.

Later, the news was everywhere that MKO has been arrested and detained in prison. 1998, five years after, we heard the sad news that our own Moshood Kasimawo Olawale gave up the ghost. 

It was believed that MKO was killed by the government, by those who forgot that one day they will also die. 

Abiola was one of the warriors who fought for democracy in Nigeria. 

May he rest in peace and may God guide, protect those alive.

Amen.

Check out www.yobamoodua.org for more on Yorùbá education and information.

Friday, June 7, 2013

ÌYÀWÓ ILÉ ILẸ̀Ẹ YORÙBÁ (THE YORÙBÁ HOUSEWIFE)

yá ni wúrà iye bíye
tí a ò lè fowó rà,
Ó lóyún mi fóṣù msaan,
ó pọ̀n mi fọ́dún mta
ìyá ni wúrà iye bíye
tí a ò lè fowó rà"

<translation>
Mother is gold, expensive,
that money cannot buy
she carried me in her womb for 9 months
she back snuggled me for 3 years.
Mother is gold, expensive,
that money cannot buy


              .................

              .................

Ìyá- is the word for mother in Yorùbá. It is believed that the African mother, the Yorùbá woman is precious and must be adored, pampered (gbe gẹ̀gẹ̀) which is why my people say 'ì ni wúrà...' (mother is gold).


Again, to the Yorubas, the 9 months;oṣù msan pregnancy stage is not an easy task, not to mention the irora- pain, stress- ìnira on the ọjọ́ ìkúnlẹ̀: day of delivery (labour). 


She has a lot on her hand to do in the welfare of her child/children (ọmọ) , she breast feeds the child "á á fún ọmọ lọ́yàn",back snug the child "á á pọn sẹ́yìn", bathe it á wẹ̀ fún un  and care for it á tọ́ júu ẹ̀ even in the middle of the night; ọ̀gànj́ òru.

The poem my mother by Ann Taylor is not enough to show the worth iyì, strength agbára of the African Yorùbá mother.

This is why in Yorùbá land, the ìyá is regarded as the next after God. Any child who disobeys the mother automatically disobeys the creator. This can also be found in the christian philosophy as well as in Islam, both the Bible & Quran attest to this. 

Ìyàwó means wife in English, while ilé is the Yoruba word for house, home and to have a 'wife' is to have a mother who knows the value of child care, home keep to list a few.

The ìyàwó ilé is the housewife, who is most of the time expected to be in the home environment and not too far from the home where the ilé ìdáná, kitchen is her main spot. When not in the ilé ìdáná, she is in the market place; ọjà  selling her wares, which includes, aṣọ-òkè, òfì (clothing), agb̀n (basket), ìkòkò; clay pots and other goods.

The ìyàwó ilé on the other hand, is what the Yoruba tradition expects the wife to be in the ilé: house. She is expected to dáná/se oúnjẹ: cook for the family, see to their well being.

The major responsibilities of an ìyàwó ilé should do include: ọmọ bíbí, child bearing, ìtọjú ọmọ àti ọkọ: child care & husband pampering, iṣẹ́ ilé: house shores.

Apart from looking after children and the other duties of the ìyàwó ilé, it is her responsibility to inculcate the Yorùbá morals, ethics, values and norms in them (ìwà ọmọlúàbí, àà, ìé ilẹ́ Yorùbá ). Of which, ìtẹríba: respect/obedience for the bí: family, ọ̀rẹ́: friends, abálégbé: neighbours, alàgbà: elders, ẹgbẹ́: age mate, is of paramount importance (ó e kókó). 

Our people often say that "ọmọ gb́dọ̀ yàn kó yanjú, ó gb́dọ̀ jẹ ọmọlúàbí, tí a bíre, t́re, wò re" - a child must be nurtured with the proper ethical, moral, social manners and for this to happen, the mother would have done a great job for her children to be regarded as ọmọlúàbí or ọmọ tó gbà ẹ̀ḱ ilé (moral children).

As the house keeper- alámójúto ilé, nothing kept in her care must go amiss, she must be a good cook for her husband to love her, she washes the man's aṣọ, clothes with that of the children if they are still in a tender age.

If a housewife did not meet up with the expectations of the bí ọkọ: husband's family (in-laws), then arises complaints over everything she does. They will say 'ìyàwó kò mọ̀ ẹsẹ gbé'.

To be loved by her in-laws;bí ọkọ, she must care for and also have respect - ìtẹ́ríba for everyone even the youngest of them (àbúrò ọkọ). She calls the male - kùnrin 'brother' and female - obìnrin 'sister' using "ẹ" as a sign of respect when she addresses them.

Are you a housewife? What shores do you do which is not stated here? Do you think the housewife still work in this generation? 

Kí lo rò? Jẹ́ kí á gb́ ní pà ẹ̀

:)


Check out www.yobamoodua.org for more on Yorùbá education and information.